Àyẹ ̀wò Ìlò Àpólà- Orúkọ Aṣẹ̀dá Nínú Ìwé Ìtànàròsọ Àjà Ló Lẹrù
Ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀ dá-èdè (linguistics) àti lítíréṣọ̀ ti wọnú ara wọn tí ó jẹ́ pé a fẹ́ rẹ̀ má le ya ọ̀ kan kúrò lára èkejì. Èròǹgbà iṣẹ́ yìí ni láti fi ìbáṣepọ̀ tí ó wà láàárin ìmọ̀ ẹ̀dá-èdè àti lítíréṣọ hán. Láti ṣe èyí a yan ìwé-ìtàn –àròsọ Àjà Ló Lẹrù tí Òkédìjí kọ láàyò, a sì fi ẹ̀ka -ẹ̀kọ́ ìmọ̀ mọ...
Saved in:
Main Authors: | , |
---|---|
Format: | Article |
Language: | English |
Published: |
LibraryPress@UF
2021-12-01
|
Series: | Yoruba Studies Review |
Online Access: | https://ojs.test.flvc.org/ysr/article/view/130089 |
Tags: |
Add Tag
No Tags, Be the first to tag this record!
|