Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà
Ọ̀pọ̀ ọ̀ nà ni àwọn onímọ̀ ti dá lábàá fún síṣe àwárí tàbí ìṣẹ̀ dá ọ̀ rọ̀ -ìperí nínú èdè Yorùbá, lára wọn ni ìsàlàyé, ìhun-ọ̀rọ̀-pọ̀ , ìfisàpẹrẹ, ìlòwe, ọ̀ rọ̀ -àyálò, ìfẹ[1]ìtumọ̀ -lójú àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ. Ìfẹ-ìtumọ̀ lójú ni ó jẹ ìwádìí yìí lógún nípa wíwá ọ̀ rọ̀ ìperí fún àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-...
Saved in:
| Main Author: | |
|---|---|
| Format: | Article |
| Language: | English |
| Published: |
LibraryPress@UF
2021-12-01
|
| Series: | Yoruba Studies Review |
| Online Access: | https://ojs.test.flvc.org/ysr/article/view/130095 |
| Tags: |
Add Tag
No Tags, Be the first to tag this record!
|
| _version_ | 1849302889399320576 |
|---|---|
| author | Clement Odoje |
| author_facet | Clement Odoje |
| author_sort | Clement Odoje |
| collection | DOAJ |
| description |
Ọ̀pọ̀ ọ̀ nà ni àwọn onímọ̀ ti dá lábàá fún síṣe àwárí tàbí ìṣẹ̀ dá ọ̀ rọ̀ -ìperí nínú èdè Yorùbá, lára wọn ni ìsàlàyé, ìhun-ọ̀rọ̀-pọ̀ , ìfisàpẹrẹ, ìlòwe, ọ̀ rọ̀ -àyálò, ìfẹ[1]ìtumọ̀ -lójú àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ. Ìfẹ-ìtumọ̀ lójú ni ó jẹ ìwádìí yìí lógún nípa wíwá ọ̀ rọ̀ ìperí fún àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara ̣ (KASA) àti Èbólà. A ṣe àgbéyẹ̀ wò 1572 ọ̀ rọ̀ tí Yusuff, Adétúnjí àti Odoje (2017) jẹ́ olóòtú fún, a sì fa àwọn tí wọ́ n fẹ ìtumọ̀ wọn lójú yọ fún ìṣẹ́ ìwádìí ti wa. A ṣàwárí pé oríṣìí mẹ́ tà ọ̀ tọ̀ ọ̀ tọ̀ ni irú àwọn ọ̀ rọ̀ yìí; kò sì sí ìyọnu láti ní òye ìtumọ̀ tuntun tí a wà wọ àwọn ọ̀ rọ̀ náà lọ́ rùn. Ó tilẹ̀ mú ìtumọ̀ gbéetán bá àwọn ọ̀ rọ̀ tuntun tí a lò wọ́ n fún.
|
| format | Article |
| id | doaj-art-562cf8c07ad045b89b60a384d94f545b |
| institution | Kabale University |
| issn | 2473-4713 2578-692X |
| language | English |
| publishDate | 2021-12-01 |
| publisher | LibraryPress@UF |
| record_format | Article |
| series | Yoruba Studies Review |
| spelling | doaj-art-562cf8c07ad045b89b60a384d94f545b2025-08-20T04:02:05ZengLibraryPress@UFYoruba Studies Review2473-47132578-692X2021-12-0161Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà Clement Odoje0University of Ibadan Ọ̀pọ̀ ọ̀ nà ni àwọn onímọ̀ ti dá lábàá fún síṣe àwárí tàbí ìṣẹ̀ dá ọ̀ rọ̀ -ìperí nínú èdè Yorùbá, lára wọn ni ìsàlàyé, ìhun-ọ̀rọ̀-pọ̀ , ìfisàpẹrẹ, ìlòwe, ọ̀ rọ̀ -àyálò, ìfẹ[1]ìtumọ̀ -lójú àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ. Ìfẹ-ìtumọ̀ lójú ni ó jẹ ìwádìí yìí lógún nípa wíwá ọ̀ rọ̀ ìperí fún àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara ̣ (KASA) àti Èbólà. A ṣe àgbéyẹ̀ wò 1572 ọ̀ rọ̀ tí Yusuff, Adétúnjí àti Odoje (2017) jẹ́ olóòtú fún, a sì fa àwọn tí wọ́ n fẹ ìtumọ̀ wọn lójú yọ fún ìṣẹ́ ìwádìí ti wa. A ṣàwárí pé oríṣìí mẹ́ tà ọ̀ tọ̀ ọ̀ tọ̀ ni irú àwọn ọ̀ rọ̀ yìí; kò sì sí ìyọnu láti ní òye ìtumọ̀ tuntun tí a wà wọ àwọn ọ̀ rọ̀ náà lọ́ rùn. Ó tilẹ̀ mú ìtumọ̀ gbéetán bá àwọn ọ̀ rọ̀ tuntun tí a lò wọ́ n fún. https://ojs.test.flvc.org/ysr/article/view/130095 |
| spellingShingle | Clement Odoje Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà Yoruba Studies Review |
| title | Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà |
| title_full | Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà |
| title_fullStr | Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà |
| title_full_unstemmed | Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà |
| title_short | Ìfẹ-ìtumọ̀-lójú: Wíwá Ọ̀rọ̀-Ìperí Fún Àrùn Kòkòrò-Apa-Sójà-Ara (KASA) àti Èbólà |
| title_sort | ife itumo loju wiwa oro iperi fun arun kokoro apa soja ara kasa ati ebola |
| url | https://ojs.test.flvc.org/ysr/article/view/130095 |
| work_keys_str_mv | AT clementodoje ifeitumolojuwiwaoroiperifunarunkokoroapasojaarakasaatiebola |